07/08/2026
Ọ̀ṢUN-ÒṢOGBO
Ọdún Ọ̀ṣun-Òṣogbo máa ń wáyé ní Oṣù Kẹjọ̀ (Ògún) lọ́dọọdún ní ìlú Òṣogbo, ó jẹ́ ọdún ìbílẹ̀ ajẹmáṣà ní ilẹ̀ Yorùbá àti orílẹ̀èdè Nàìjíríà lápapọ̀. Òrìṣà Ọ̀ṣun Ṣẹ̀ǹgẹ̀ṣẹ́ Ọlọ́mọyọyọ, tí a a mọ̀ mọ́ omi, ìṣabiyamọ, ìlọsíwájú àti ìgbéga ìlú. ni wọ́n fi ọdún yín sọrí. Lara àwọn ìṣẹ̀lẹ̀ pàtàkì tí ó máa ń wáyé lásìkò ọdún náà ni kí Arugbá Ọ̀ṣun ru igbá lọ sí Igbó Ọ̀ṣun Arugbá ń ru igbá. Lọ́dọọdún ni àwọn olùsìn, arìnrìn-àjò afẹ́, aṣèwádìí àti àwọn olùfẹ́ àṣà máa ń péjú-pésẹ̀ níbi ayẹyẹ ọdún náà. Osun Òṣogbo kẹnu tayọ ọdún lásán, ó ń ṣàfihàn ìtàn, ẹsìn, ìdánimọ̀, àjogúnbá ajẹmáṣà tí à ń ṣe lọ́jọ́ láti ìrandíran.
The Osun-Osogbo Festival takes place every August in Osogbo, Osun State, Nigeria, and is one of the most celebrated traditional festivals in Yorùbáland. The festival honours Osun, the Yorùbá river deity associated with water, fertility, motherhood, prosperity, and the well-being of the community. One of its most significant traditions is the procession of the Arugbá. Every year, devotees, tourists, researchers, and culture enthusiasts gather in Osogbo to witness the festival and experience its rich traditions. More than
an annual celebration, Osun-Osogbo is a living expression of Yorùbá history, spirituality, identity, and cultural heritage, preserved and passed down from one generation to another.
Oreyèyé Ọ̀ṣun oooo!